Adekunle Gold

Adekunle Gold
Orúkọ àbísọAdekunle Kosoko
Ọjọ́ìbí28 Oṣù Kínní 1987 (1987-01-28) (ọmọ ọdún 38)
Lagos State
Irú orin
Occupation(s)
Instruments
Years active2010–present
Associated acts
Websiteadekunlegold.com

Adekunle Almoruf Kosoko (tí a bí ní Oṣù Kìíní Ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n, Ọdún 1987), tí a mọ̀ gẹ́gẹ́ bíi Adekunle Gold àti AG Baby, jẹ́ olórin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, akọrin sílẹ̀ ati ayàwòrán. [1] Ó di ìlúmọ̀ọ́ká olórin lẹ́yìn tí ó kọ orin kan tí a mọ̀ sí “Ṣadé” ní ọdún 2015. Ní ọdún 2015, ó fọwọ́síwèé àdéhùn ìgbàsílẹ̀ pẹ̀lú YBNL Nation tí ó sì gbé orin [[studio]] kan jáde tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ Gold, èyí tí ó wà ní ipò keje ti Billboard àgbáyé. Ṣáájú Gold ni ó ti kọ àwọn orin mẹ́ta kan tí àkọ́lé wọn ń jẹ́ "Sade", "Orente" ati "pick up". Adekunle Gold fi hàn sí Ilé Ìdanilárayá Nàìjíríà lónìí pé ṣáájú kí ó tó f'ọwọ́ sí pẹ̀lú YBNL, ó ṣe àpẹẹrẹ aami ti ilé-iṣẹ́ náà àti pé ó parí àwọn àpẹẹrẹ mìíràn fún Lil Kesh, Viktoh àti Olamide.[2]

Adekunle Gold
  1. "I didn’t lobby to be signed by Olamide – Adekunle Gold". 12 August 2015. http://www.vanguardngr.com/2015/08/i-didnt-lobby-to-be-signed-by-olamide-adekunle-gold/. Retrieved 29 October 2015. 
  2. Kayode Badmus (21 August 2015). "I was involved with YBNL before Olamide signed me – Adekunle Gold". Nigerian Entertainment Today. Archived from the original on 21 August 2015. 

From Wikipedia, the free encyclopedia · View on Wikipedia

Developed by Nelliwinne