Akinwunmi Ambode

Akínwùnmí Aḿbọ̀dé (tí a bí ní Ọ̣jọ́ Kẹrìnlá Oṣù Kẹfà Ọdún 1963) jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó láàrin ọdún 2015 sí 2019.[1] Ó ti fìgbà kan jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n. Ó jẹ́ Olùgbaninímọ̀ràn lórí ìsúnná owó kí ó tó wá díje dupò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Èkó ní ọdún 2015.

Akínwùnmí Aḿbọ̀dé
14th Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó
In office
29 May 2015 – 29 May 2019
DeputyIdiat Adebule
AsíwájúBabatunde Fashola
Arọ́pòBabajide Sanwo-Olu
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí14 Oṣù Kẹfà 1963 (1963-06-14) (ọmọ ọdún 61)
  1. Television, Channels (April 12, 2015). "Akinwunmi Ambode Wins Lagos Governorship Election". Channels Television. Retrieved June 12, 2023. 

From Wikipedia, the free encyclopedia · View on Wikipedia

Developed by Nelliwinne