Babajide Olusola Sanwo-Olu | |
---|---|
![]() Babajide Sanwo-Olu | |
15th Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó | |
In office 29 Oṣù Kàrún 2015 – seronja | |
Deputy | Femi Hamzat |
Asíwájú | Akinwunmi Ambode |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
Education | University of Lagos Lagos Business School John F. Kennedy School of Government London Business School |
Occupation | Banker, Politician |
Babájídé Olúṣọlá Sanwó-Olú (ọjọ́-ìbí - ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n, oṣù June, ọdún 1965)[1][2][3][4] jẹ́ olóṣèlú àti Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó tó wà lórí àléfà lọ́wọ́lọ́wọ́. Wọ́n dìbò yàán gẹ́gẹ́ bí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó ní ọdún 2019 lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú APC. Lẹ́yìn tí Gómìnà àná, Ìpínlẹ̀ Èkó, Akínwùnmí Àḿbọ̀dẹ́ ìjákulẹ̀ nínú ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ All Progressive Congress. [5] [6] [7] [8]
<ref>
tag; no text was provided for refs named Babajide
<ref>
tag; no text was provided for refs named Olusola
<ref>
tag; no text was provided for refs named Sanwo-Olu