Rt. Hon. Femi Abdulhakim Gbajabiamila | |
---|---|
![]() Femi Gbajabiamila | |
Speaker of the House of Representatives of Nigeria | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga June 2019 | |
Asíwájú | Yakubu Dogara |
House Leader of the House of Representatives of Nigeria | |
In office June 2015 – June 2019 | |
Asíwájú | Ogor Okuweh |
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria | |
In office June 2011 – June 2015 | |
Arọ́pò | Ogor Okuweh |
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria | |
In office June 2007 – June 2011 | |
Asíwájú | Ahmed Salik |
Member of the House of Representatives of Nigeria | |
In office 2003–2007 | |
Asíwájú | yakubu Dogara |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 25 Oṣù Kẹfà 1962 Lagos State, Nigeria |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressive Congress (APC) |
Residence | Lagos |
Alma mater | University of Lagos |
Occupation | Legislature |
Website | http://femigbajabiamila.com |
Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 1962 (June 25, 1962) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèlú, Agbẹjọ́rò àti Agbẹnusọ Ilé-Ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú, All Progressives Congress tí ó ń ṣojú ìjọba ìbílẹ̀ Sùúrùlérè ni ìpínlẹ̀ Èkó láti ọdun 2019[1] [2] [3] [4]