Femi Gbajabiamila

Rt. Hon.

Femi Abdulhakim Gbajabiamila
Femi Gbajabiamila
Speaker of the House of Representatives of Nigeria
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
June 2019
AsíwájúYakubu Dogara
House Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2015 – June 2019
AsíwájúOgor Okuweh
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2011 – June 2015
Arọ́pòOgor Okuweh
Minority Leader of the House of Representatives of Nigeria
In office
June 2007 – June 2011
AsíwájúAhmed Salik
Member of the House of Representatives of Nigeria
In office
2003–2007
Asíwájúyakubu Dogara
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí25 Oṣù Kẹfà 1962 (1962-06-25) (ọmọ ọdún 62)
Lagos State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress (APC)
ResidenceLagos
Alma materUniversity of Lagos
OccupationLegislature
Websitehttp://femigbajabiamila.com

Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 1962 (June 25, 1962) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèlú, Agbẹjọ́rò àti Agbẹnusọ Ilé-Ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú, All Progressives Congress tí ó ń ṣojú ìjọba ìbílẹ̀ Sùúrùlérè ni ìpínlẹ̀ Èkó láti ọdun 2019[1] [2] [3] [4]

  1. "THISDAYonline". BNW News. Archived from the original on 2020-01-13. Retrieved 2020-01-13. 
  2. Assembly, Nigerian National (1962-06-25). "Federal Republic of Nigeria". National Assembly. Retrieved 2020-01-13. 
  3. "When encomiums poured in torrents for Femi Gbajabiamila in Lagos". Premium Times Nigeria. 2012-06-27. Retrieved 2020-01-13. 
  4. "Ahmed Lawan, Femi Gbajabiamila go lead Nigeria 9th National Assembly". BBC News Pidgin (in Kúẹ́ńjùà). 2019-06-11. Retrieved 2020-01-13. 

From Wikipedia, the free encyclopedia · View on Wikipedia

Developed by Nelliwinne