Nigerian Law School jẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ tí ìjọba gbé kalẹ̀ ní ọdún 1962 fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ́ìmọ̀ Òfin yálà ní ́abẹ́lé ni tàbí fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ òkè-òkun ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Àwọn tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ sí iṣẹ́ ìmọ̀ òfin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣáájú ọdún 1962 ti ìjọba gbé ilé-ẹ̀kọ́ yi kalẹ̀ ni wọ́n ma ń lọ kọ́ èkọ́ ìmọ̀ òfin ní orílẹ-èdè England tí wọn sì ma ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi amòfin ní ìlú náà .[2]
<ref>
tag; no text was provided for refs named self
|url-status=
ignored (help)