Zack Orji

Zack Orji
Ọjọ́ìbíZachee Ama Orji
1960 (ọmọ ọdún 64–65)
Libreville, Gabon
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iléẹ̀kọ́ gígaUniversity of Nigeria Nsukka
Iṣẹ́Actor-Director
Ìgbà iṣẹ́1991-present
Gbajúmọ̀ fúnRole in Glamour Girls, and Blood Money.
Olólùfẹ́Ngozi Orji
Àwọn ọmọ3

Zachee Ama Orji (tí wọ́n bí ní ọdún 1960) jẹ́ òṣèrékùnrin, olùdarí, aṣagbátẹrù fíìmù ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà[1][2] tí ó gbajúmọ̀ fún ìkópa rẹ̀ nínú fíìmù Glamour Girls, àti Blood Money. Yàtọ̀ sí eré-ṣíṣe, Orji jẹ́ oníwàásù.[3]

  1. Adebayo, Tireni (21 October 2017). "Veteran actor, Zack Orji reveals his battle with cigarettes and Indian hemp". Kemi Filani News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 12 March 2022. 
  2. "Zack Orji: My life as an actor, singer and preacher of God's word". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 29 February 2020. Retrieved 18 July 2022. 
  3. "Zack Orji: My life as an actor, singer and preacher of God's word". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 29 February 2020. Retrieved 25 July 2022. 

From Wikipedia, the free encyclopedia · View on Wikipedia

Developed by Nelliwinne